Ọ̀kan nínú àwọn ọ̀gá Ọlọpa ilẹ̀ yí DCP Bassey Ewah, ti kìlọ̀ fún àwọn ọmọ orile-ede Naijiria lọ́jọ́rú tí ó kọjá yí wípé ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ yàǹda ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká rẹ fún Ọlọpa kankan níloro àyẹ̀wò àwọn Ọlọpa láláìsí ìwé àṣẹ ṣíṣe bẹ́ẹ̀. Arákùnrin yí ṣàlàyé wípé, bí Ọlọp...
Share this page with your family and friends.