To continue using the site you need to read the revised version and agree to the policies
  Thanks for your feedback. Your report has been submitted.
Ọ̀kan nínú àwọn ọ̀gá Ọlọpa ilẹ̀ yí DCP Bassey Ewah, ti kìlọ̀ fún àwọn ọmọ orile-ede Naijiria lọ́jọ́rú tí ó kọjá yí wípé ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ yàǹda ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká rẹ fún Ọlọpa kankan níloro àyẹ̀wò àwọn Ọlọpa láláìsí ìwé àṣẹ ṣíṣe bẹ́ẹ̀. Arákùnrin yí ṣàlàyé wípé, bí Ọlọp...
