Ọ̀kan nínú àwọn ondije dupò Ààrẹ ọdún 2019 nínú ètò ìdìbò gbogbogbò tó kọjá Comrade Ademola Babatunde Abidemi Samuel ti bu ẹnu àtẹ́ lu ọ̀pọ̀ ọmọ orile-ede Naijiria tó ń ro ikú ro Ààrẹ Muhammad Buhari. Arákùnrin yi ṣe é lálàyé wípé òun lè fi irúfé àwọn ẹ̀dá bẹ́ẹ̀ wé àwọn janduku a...
Share this page with your family and friends.