To continue using the site you need to read the revised version and agree to the policies
  Thanks for your feedback. Your report has been submitted.
Ọ̀kan nínú àwọn ondije dupò Ààrẹ ọdún 2019 nínú ètò ìdìbò gbogbogbò tó kọjá Comrade Ademola Babatunde Abidemi Samuel ti bu ẹnu àtẹ́ lu ọ̀pọ̀ ọmọ orile-ede Naijiria tó ń ro ikú ro Ààrẹ Muhammad Buhari. Arákùnrin yi ṣe é lálàyé wípé òun lè fi irúfé àwọn ẹ̀dá bẹ́ẹ̀ wé àwọn janduku a...
